Font Size
Matiu 15:4
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Matiu 15:4
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
4 Nítorí Ọlọ́run wí pé, ‘Bọ̀wọ̀ fún Baba òun ìyá rẹ,’ àti pé, ‘Ẹnikẹ́ni tí ó bá sọ ọ̀rọ̀-òdì sí baba tàbí ìyá rẹ̀, ní láti kú.’
Read full chapter
Marku 7:10
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Marku 7:10
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
10 (A)Mose fún un yín ní òfin yìí láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run pé, ‘Bọ̀wọ̀ fún baba òun ìyá rẹ.’ Ó tún sọ pé, ‘Ẹnikẹ́ni tí ó bá sọ̀rọ̀ aburú sí baba tàbí ìyá rẹ̀ ní láti kú ni.’
Read full chapter
Efesu 6:3
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Efesu 6:3
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
3 (A)“ki ó lé dára fún ọ, àti kí ìwọ lè wà pẹ́ ní ayé.”
Read full chapter
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn (BYO)
Copyright: Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní Ẹ̀tọ́ àdàkọ © 2009, 2017 by Biblica, Inc. A lò ó nípa ìgbàyọ̀ǹda láti ọwọ́ Bíbílíkà Inc. Ààbò lórí ẹ̀tọ́ àdàkọ yìí múlẹ̀ jákèjádò àgbáyé. Yoruba Contemporary Bible Copyright © 2009, 2017 by Biblica, Inc.® Used by permission of Biblica, Inc.® All rights reserved worldwide.