Font Size
Jeremiah 10:7
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Jeremiah 10:7
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
7 Ta ni kò yẹ kí ó bẹ̀rù rẹ ọba àwọn
orílẹ̀-èdè? Nítorí tìrẹ ni, láàrín àwọn
ọlọ́gbọ́n ènìyàn ní orílẹ̀-èdè àti
gbogbo ìjọba wọn, kò sí ẹni tí ó dàbí rẹ.
Saamu 86:9-10
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Saamu 86:9-10
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
9 Gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè tí ìwọ dá
yóò wá, láti wá jọ́sìn níwájú rẹ, Olúwa;
wọn ó mú ògo wà fún orúkọ rẹ̀.
10 Nítorí pé ìwọ tóbi, ìwọ sì ń ṣe ohun ìyanu;
ìwọ nìkan ni Ọlọ́run.
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn (BYO)
Copyright: Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní Ẹ̀tọ́ àdàkọ © 2009, 2017 by Biblica, Inc. A lò ó nípa ìgbàyọ̀ǹda láti ọwọ́ Bíbílíkà Inc. Ààbò lórí ẹ̀tọ́ àdàkọ yìí múlẹ̀ jákèjádò àgbáyé. Yoruba Contemporary Bible Copyright © 2009, 2017 by Biblica, Inc.® Used by permission of Biblica, Inc.® All rights reserved worldwide.