Add parallel Print Page Options

Ṣé báyìí ni ẹ̀yin yóò ṣe san an fún Olúwa,
    Háà, ẹ̀yin aṣiwèrè àti aláìgbọ́n ènìyàn?
Ǹjẹ́ òun kọ́ ni baba yín, Ẹlẹ́dàá yín,
    tí ó dá a yín tí ó sì mọ yín?

Read full chapter

16 Ṣùgbọ́n ìwọ ni baba wa,
    bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé Abrahamu kò mọ̀ wá
tàbí Israẹli mọ ẹni tí à á ṣe;
    ìwọ, Olúwa ni Baba wa,
    Olùràpadà wa láti ìgbà n nì ni orúkọ rẹ.

Read full chapter

Síbẹ̀síbẹ̀, Olúwa, ìwọ ni Baba wa.
    Àwa ni amọ̀, ìwọ ni amọ̀kòkò;
    gbogbo wa jẹ́ iṣẹ́ ọwọ́ rẹ.

Read full chapter